Yoruba Paper 2 WASSCE (PC), 2021

Question 8

 

 

Sọ̀rọ̀ lórí ìwúlò Ègè

Observation

 

 

Candidates were required to discuss the importance of Ègè Dídá as evident in the excerpt.

 

          Iwúlò Ègè:

(i)      Ègè dídá kún fún ìjìnlẹ̀ ọ̀rọ̀, ọgbọ́n àti ọ̀rọ̀ apanilẹ́rìn-ín
(ii)      Ègè dídá máa ń dá ènìyàn lára yá 
(iii)     Ó máa ń rán ènìyàn léti ìṣẹ̀lẹ̀ tí ó ti kọ́já tàbí ìtàn tí ó fara sin láti fi kọ́ àwọn èrò ìwòran lẹ́kọ̀ọ́
(iv)     Ó máa ń mú orí ẹni wú/yá
(v)      Ó jẹ́ ọ̀nà àtijẹ fún àwọn tí ó fi ń ṣe iṣẹ́ ṣe
(vi)     Ó máa ń fọ àwujọ́ mọ́ nípa ṣíṣe àfihàn ìwà ìbàjẹ́/kòtọ́ ní àwùjọ
(vii)    Ó máa ń ki ènìyàn nílọ̀ lórí ìwà kòtọ́
(viii)   Ègè wà fún ayẹyẹ gbogbo láti mú ìgbádùn bá àwùjọ
(ix)     Ó wúlò fún ìpolon̄go onírúurú nǹkan láwùjọ Yorùbá
(x)      Àwọn Yorùbá máa ń lo Ègè gẹ́gẹ́ bí orin amúṣẹ́yá.

 

Only a few candidates attempted this question.  Their responses to this question portrayed failure to study the text.